Babagana Umara Zulum

Olóṣèlú From Wikipedia, the free encyclopedia

Ọ̀jọ̀gbọ́n Babagana Umara Zulum tí wọ́n bí ní Ọjọ́ kẹrìndínlọ́gbọ̀n oṣù kẹjọ ọdún 1969 (August 26th, 1969) jẹ́ ọ̀jọ̀gbọ́n àti olóṣèlú ọmọ bíbí ìpínlẹ̀ Borno lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà. Òun ni Gómìnà Ìpínlẹ̀ Born Lọ́wọ́lọ́wọ́. Wọ́n dìbò yàn án lọ́dún 2019 lábẹ́ àsíyá ẹgbẹ́ òṣèlú APC.[1][2]

Quick Facts Gómìnà Ìpínlẹ̀ Bọ̀rnó, Asíwájú ...
Babagana Umara Zulum
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Bọ̀rnó
Lọ́wọ́lọ́wọ́
Ó gun orí àga
29 May 2019
AsíwájúKashim Shettima
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí26 Oṣù Kẹjọ 1969 (1969-08-26) (ọmọ ọdún 55)
Mafa
Ọmọorílẹ̀-èdèNigerian
Ẹgbẹ́ olóṣèlúAll Progressive Congress (APC)
Websitezulum.ng
Close

Ìgbà èwe rẹ̀

Gẹ́gẹ́ bí a ti sọ ṣáájú, wọ́n bí Babagana lọ́jọ́ kẹrìndínlọ́gbọ̀n oṣù kẹjọ ọdún 1979 ní Ìjọba Ìbílẹ̀ Mafa ní Ìpínlẹ̀ Borno .[3]

Àwọn Ìtọ́kasí

Loading related searches...

Wikiwand - on

Seamless Wikipedia browsing. On steroids.