Olóṣèlú From Wikipedia, the free encyclopedia
Amina Jane Mohammed tí a bí ní 27 June 1971 jé olósèlú omo orílè-èdè Nàìjíríà àti orílè-èdè Britain, òun ígbákejì akowe fun Igbimọ gbogboogbo ti orilẹ-ede Agbaye(United Nations) lowolowo,[2] laarin odun 2015 sí 2016, òun ni lo jé minisita Nàìjíríà fun ètó adugbo.[3]
Her Excellency Amina J. Mohammed | |
---|---|
Amina J. Mohammed ní London ní ọdun 2018 | |
Deputy Secretary-General of the United Nations | |
Lọ́wọ́lọ́wọ́ | |
Ó gun orí àga 28 February 2017[1] | |
Secretary-General | António Guterres |
Asíwájú | Jan Eliasson |
Minister of Environment | |
In office 11 November 2015 – 15 December 2016 | |
Ààrẹ | Muhammadu Buhari |
Asíwájú | Lawrencia Laraba-Mallam |
Arọ́pò | Ibrahim Usman Jibril |
Àwọn àlàyé onítòhún | |
Ọjọ́ìbí | Amina Jane Mohammed 27 Oṣù Kẹfà 1961 Liverpool, England |
Aráàlú | |
Education | The Buchan School |
Alma mater | Henley Management College |
A bí Amina Jane Mohammed ni ojo June 27, 1961 ní ìlú Liverpool, England ní orílè-èdè United Kingdom.[4] Baba rè jé Hausa-Fulani, òsì jé Dókítá alabare àwon eranko, Ìyá rè sì jé Noosi omo orílè-èdè United Kingdom. Amina ni omo àkókó larin omo marun.[5]
Mohammed lo ilé-ìwé Primari ní ìpínlè Kaduna, o sì tèsíwájú ní ilé-ìwé Buchan ní orílè-èdè Isle of Man fún ìwé sekondori rè.[3] O tún tèsíwájú ní Henley Management College ni odún 1989. Léyìn tí o parí èkó rè, bàbá rè so pé kí o padà sí Nàìjíríà.[5]
Larin 1981 sí 1991, Mohammed sísé pèlú ilé-isé Archon Nigeria, ilé-isé tí oun yaworan ilé. Ni odun 1991, Mohammed dá ilé-isé Afri-projects Consortium kalè, larin odun 1991 sí odun 2001, oun ni adari àti apase ilé-isé náà.[6]
Seamless Wikipedia browsing. On steroids.
Every time you click a link to Wikipedia, Wiktionary or Wikiquote in your browser's search results, it will show the modern Wikiwand interface.
Wikiwand extension is a five stars, simple, with minimum permission required to keep your browsing private, safe and transparent.