From Wikipedia, the free encyclopedia
Oba Oyekan I (ó kú ní ọjọ́ ogbọ̀n oṣù Kẹ̀sán ọdún 1900) joba gẹ́gẹ́ bí Ọba ìlú Èkó láti oṣù kẹta ọdún 1885 sí ọjọ́ ogbọ̀n oṣù Kẹ̀sán ọdún 1900. Ó gun orí ìtẹ́ lẹ́yìn oṣù kan tí bàbá rẹ̀ Oba Dosunmu kú.[1]
Oba Oyekan I | |
---|---|
Ọba ìlú Èkó | |
Oba of Lagos | |
Reign | 1885 - 1900 |
Coronation | 1885 |
Predecessor | Dosunmu |
Successor | Eshugbayi Eleko |
House | Akitoye, Dosunmu |
Father | Oba Dosunmu |
Born | 1871 Lagos, Nigeria |
Died | September 30, 1900 Lagos |
Burial | Iga Idunganran |
Ní 1883, Oba Dosunmu, bàbá Oyekan pe ìpàdé láti wo wàhálà láàrin Olóyè Apena Ajasa àti Olóyè Taiwo Olowo síbẹ̀síbẹ̀ Olóyè Ajasa ń halẹ̀ sí Ọba àti àwọn ìjòyè tó kù. Nígbà tí o ń wo ipò tí Apena Ajasa fí ń halẹ̀, ọmọ ọba Oyekan gbá Olóyè Ajasa ní etí tí ó sì sọ pé Ajasa ko yẹ kí o bú Ọba ni Iga Idunganran (ààfin Ọba). Ọba Dosunmu ko gba ìwà Oyekan, ó si bù lépè pé" Ọmọkùnrin tó ti hùwà báyìí kí o sọnù" . Olóyè Taiwo Olowo, orogún Olóyè Apena Ajasa inú re dun nípa ìgbésí Oyekan, o sì kojú ète sí Oba Dosunmu wí pé" Ọmọkùnrin náà kò ní ṣófo ṣùgbọ́n ẹ̀mí rẹ yóò gùn" [2]
Ọba Oyekan kú ní ọjọ́ ìṣẹ́jú, oṣù kẹsàn-án ọdún 1900 lẹ́yìn ìgbà tí ó ṣe àìsàn fún ìgbà díẹ̀. Ó jọba fún ọdún mẹ́ẹ̀ẹ́dógún (15) gẹ́gẹ́ bí Ọba ti Èkó. [3]
Seamless Wikipedia browsing. On steroids.
Every time you click a link to Wikipedia, Wiktionary or Wikiquote in your browser's search results, it will show the modern Wikiwand interface.
Wikiwand extension is a five stars, simple, with minimum permission required to keep your browsing private, safe and transparent.