National Museum tí orílè-èdè Nàìjíríà
From Wikipedia, the free encyclopedia
Musiomu Orilẹ-ede Naijiria jẹ ile musiọmu ní ìpínlè Èkó, orílè-èdè Nàìjíríà Ile-išẹ musiọmu naa ni akojọpọ àwon ère ati aworan nlá ni Naijiria, pẹlu awọn awọn ohun-ọṣọ. [1] Musiomu náà wa ni Onikan, Lagos Island, Ipinle Eko. Ówà labé idari National Commission for Museums and Monuments.